Repository logo
  • English
  • Català
  • Čeština
  • Deutsch
  • Español
  • Français
  • Gàidhlig
  • Latviešu
  • Magyar
  • Nederlands
  • Polski
  • Português
  • Português do Brasil
  • Suomi
  • Svenska
  • Türkçe
  • Қазақ
  • বাংলা
  • हिंदी
  • Ελληνικά
  • Yкраї́нська
  • Log In
    New user? Click here to register.Have you forgotten your password?
Repository logo
  • Communities & Collections
  • All of DSpace
  • English
  • Català
  • Čeština
  • Deutsch
  • Español
  • Français
  • Gàidhlig
  • Latviešu
  • Magyar
  • Nederlands
  • Polski
  • Português
  • Português do Brasil
  • Suomi
  • Svenska
  • Türkçe
  • Қазақ
  • বাংলা
  • हिंदी
  • Ελληνικά
  • Yкраї́нська
  • Log In
    New user? Click here to register.Have you forgotten your password?
  1. Home
  2. Browse by Author

Browsing by Author "Hakeem Olawale"

Now showing 1 - 20 of 21
Results Per Page
Sort Options
  • Loading...
    Thumbnail Image
    Item
    Àgbéyẹ̀wò Ìlò-Èdè Nínú Orin Ìbílẹ̀ Ìlọrin
    (2021) Hakeem Olawale
    Ọ̀kan pàtàkì tí kò ṣe é fọwọ́ rọ́ sẹ́yìn lára ẹ̀ka tí lítíréṣọ̀ alohùn Yorùbá pín sí ni orin jẹ́. Bárakú sì ní ọ̀rọ̀ orin láwùjọ ọmọ ènìyàn pàápàá jù lọ àwọn Yorùbá nítorí pé onírúurú ààyè ni orin ti máa ń jẹ jáde nínú ìgbésí-ayé wọn lójoojúmọ́. Bí àwọn akọrin àwùjọ bá sì ń ṣiṣẹ́ ọnà wọn, ìjìnlẹ̀ èdè tó jinná ni wọ́ n fi máa ń gbé e jáde tí yóò sì máa ṣàfihàn bí irú àwọn akọrin bẹ́ ẹ̀ ṣe gbọ́ èdè àti ìmọ̀ nípa àṣà àwùjọ tó ti ń kọrin nítorí pé ìpohùn ìbílẹ̀ èyí tí orin jẹ́ ọ̀ kan pàtàkì lára wọn dà gẹ́gẹ́ bí àwògbè tàbí díńgí tí a fi ń ríran rí àwùjọ. Ìlò-èdè tó jinná kò sì ṣe é fọwọ́ rọ́ sẹ́yìn kí àgbékalẹ̀ orin wọ̀nyẹn lè rídìí jòkó dáadáa kí wọ́n sì lè wu etí í gbọ́. Nínú iṣẹ́ yìí, a ṣe àgbéyẹ̀wò àtí àtúpalẹ̀ díẹ̀ lára àwọn ọnà-èdè tó ṣúyọ nínú àṣàyàn orin ìbílẹ̀ Yorùbá Ìlọrin bíi dàdàkúàdà, bàlúù, wákà, kèǹgbè, sẹnwẹlẹ, kàkàkí/bẹ̀ ǹbẹ́ , Orin ọlọ́ mọ-ọba Ìlọrin,orin agbè àti àwọn mìíràn. Lára àwọn ọnà-èdè tí a gbéyẹ̀ wò ni àwítúnwí, àfiwé, ìjẹyọ ẹ̀ ka-èdè, àyálò-èdè àti ipa ‘Creole’ nínú orin ìbílẹ̀ Ìlọrin. Iṣẹ́ yìí ṣàfihàn pé iṣẹ́ ọpọlọ tó jinná ni orin kíkọ àti pé àwọn ọnà-èdè tó máa ń ṣodo sínú wọn lóríṣiríṣi ní iṣẹ́ tí kálukú wọn ń jẹ́ láti túdìí òkodoro nípa àṣà, ìṣe àti èdè àwùjọ tí onírúurú àwọn orin náà ti ń jáde
  • Loading...
    Thumbnail Image
    Item
    Àgbéyẹ̀wò Ìlò-Èdè Nínú Orin Ìbílẹ̀ Ìlọrin
    (2021) Hakeem Olawale
    Ọ̀kan pàtàkì tí kò ṣe é fọwọ́ rọ́ sẹ́yìn lára ẹ̀ka tí lítíréṣọ̀ alohùn Yorùbá pín sí ni orin jẹ́. Bárakú sì ní ọ̀rọ̀ orin láwùjọ ọmọ ènìyàn pàápàá jù lọ àwọn Yorùbá nítorí pé onírúurú ààyè ni orin ti máa ń jẹ jáde nínú ìgbésí-ayé wọn lójoojúmọ́. Bí àwọn akọrin àwùjọ bá sì ń ṣiṣẹ́ ọnà wọn, ìjìnlẹ̀ èdè tó jinná ni wọ́ n fi máa ń gbé e jáde tí yóò sì máa ṣàfihàn bí irú àwọn akọrin bẹ́ ẹ̀ ṣe gbọ́ èdè àti ìmọ̀ nípa àṣà àwùjọ tó ti ń kọrin nítorí pé ìpohùn ìbílẹ̀ èyí tí orin jẹ́ ọ̀ kan pàtàkì lára wọn dà gẹ́gẹ́ bí àwògbè tàbí díńgí tí a fi ń ríran rí àwùjọ. Ìlò-èdè tó jinná kò sì ṣe é fọwọ́ rọ́ sẹ́yìn kí àgbékalẹ̀ orin wọ̀nyẹn lè rídìí jòkó dáadáa kí wọ́n sì lè wu etí í gbọ́. Nínú iṣẹ́ yìí, a ṣe àgbéyẹ̀wò àtí àtúpalẹ̀ díẹ̀ lára àwọn ọnà-èdè tó ṣúyọ nínú àṣàyàn orin ìbílẹ̀ Yorùbá Ìlọrin bíi dàdàkúàdà, bàlúù, wákà, kèǹgbè, sẹnwẹlẹ, kàkàkí/bẹ̀ ǹbẹ́ , Orin ọlọ́ mọ-ọba Ìlọrin,orin agbè àti àwọn mìíràn. Lára àwọn ọnà-èdè tí a gbéyẹ̀ wò ni àwítúnwí, àfiwé, ìjẹyọ ẹ̀ ka-èdè, àyálò-èdè àti ipa ‘Creole’ nínú orin ìbílẹ̀ Ìlọrin. Iṣẹ́ yìí ṣàfihàn pé iṣẹ́ ọpọlọ tó jinná ni orin kíkọ àti pé àwọn ọnà-èdè tó máa ń ṣodo sínú wọn lóríṣiríṣi ní iṣẹ́ tí kálukú wọn ń jẹ́ láti túdìí òkodoro nípa àṣà, ìṣe àti èdè àwùjọ tí onírúurú àwọn orin náà ti ń jáde
  • Loading...
    Thumbnail Image
    Item
    Àgbéyẹ̀wò Ìlò-Èdè Nínú Orin Ìbílẹ̀ Yorùbá ní Ìlọrin
    (2021) Hakeem Olawale
    Ọ̀kan pàtàkì tí kò ṣe é fọwọ́ rọ́ sẹ́yìn lára ẹ̀ka tí lítíréṣọ̀ alohùn Yorùbá pín sí ni orin jẹ́. Bárakú sì ní ọ̀rọ̀ orin láwùjọ ọmọ ènìyàn pàápàá jù lọ àwọn Yorùbá nítorí pé onírúurú ààyè ni orin ti máa ń jẹ jáde nínú ìgbésí-ayé wọn lójoojúmọ́. Bí àwọn akọrin àwùjọ bá sì ń ṣiṣẹ́ ọnà wọn, ìjìnlẹ̀ èdè tó jinná ni wọ́n fi máa ń gbé e jáde tí yóò sì máa ṣàfhan bí irú àwọn akọrin bẹ́ẹ̀ ṣe gbọ́ èdè àti ìmọ̀ nípa àṣà àwùjọ tó ti ń kọrin nítorí pé ìpohùn ìbílẹ̀ èyí tí orin jẹ́ ọ̀kan pàtàkì lára wọn dà gẹ́gẹ́ bí àwògbè tàbí díńgí tí a fi ń ríran rí àwùjọ. Ìlò-èdè tó jinná kò sì ṣe é fọwọ́ rọ́ sẹ́yìn kí àgbékalẹ̀ orin wọ̀nyẹn lè rídìí jòkó dáadáa kí wọ́n sì lè wu etí í gbọ́. Nínú iṣẹ́ yìí, a ṣe àgbéyẹ̀wò àtí àtúpalẹ̀ díẹ̀ lára àwọn ọnà-èdè tó ṣúyọ nínú àṣàyàn orin ìbílẹ̀ Yorùbá Ìlọrin bíi dàdàkúàdà, bàlúù, wákà, kèǹgbè, sẹnwẹlẹ, kàkàkí/bẹ̀ǹbẹ́, Orin ọlọ́mọ-ọba ìlọrin,orin agbè àti àwọn mìíràn. Lára àwọn ọnà-èdè tí a gbéyẹ̀wò ni àwítúnwí, àfiwé, ìjẹyọ ẹ̀ka-èdè, àyálò-èdè àti ipa ‘Creole’ nínú orin ìbílẹ̀ Ìlọrin. Iṣẹ́ yìí ṣàfihàn pé iṣẹ́ ọpọlọ tó jinná ni orin kíkọ àti pé àwọn ọnà-èdè tó máa ń ṣodo sínú wọn lóríṣiríṣi ní iṣẹ́ tí kálukú wọn ń jẹ́ láti túdìí òkodoro nípa àṣà, ìṣe àti èdè àwùjọ tí onírúurú àwọn orin náà ti ń jáde.
  • No Thumbnail Available
    Item
    Challenges Facing Gàá Fúlàní Settlements in Ìlọrin Emirate and Solutions.
    (2025) Hakeem Olawale
  • No Thumbnail Available
    Item
    Ifiwadiisotumo Iyanrofere Inu Oriki Orile Awon Ilu Ajorukomo-Ifon
    (2020) Hakeem Olawale
    Philosophy of Ọbáfẹ́mi Awólọ́wọ̀ and Nation Building
  • Loading...
    Thumbnail Image
    Item
    Ìjẹyọ Ẹ̀kọ́ Ìjìnlẹ̀, Èdè, Àṣà àti Ìtàn Pàtàkì Nínú Àṣàyàn Orin Ìbílẹ̀ Ìlọrin
    (2019) Hakeem Olawale
    Onírúurú ẹ̀ka ló máa ń ṣodo sínú orin ìbílẹ̀ nítorí pé inú àwùjọ ni àwọn akọrin ń gbé tí wọ́n sì máa ń ṣàmúlò láti inú ibú ìmọ̀ wọn, ìrírí wọ àti àrọ́bá láti ẹnu àwọn babańlá wọn, èyí tí wan máa ń sọ di orin láti fi èrò ọkàn wọn hàn àti fún ìdárayá. Ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn akọrin ìbílẹ̀ ló gbọ́ èdè Yorùbá tó sì máa ń hàn nínú ìpohùn orin wọn. Ìjìnlẹ̀ èdè, àṣà ìbílẹ̀, ìyánrọ̀fẹ́ẹ́rẹ́ àti òkodoro àwọn ìtàn mìíràn tó farasin máa ń dàwárí nínú orin wọ̀nyìí tí a bá gba wọn láìwo ti adùn orin nìkan. Orin tún máa ń ṣàfihàn ìwọ́ká ìran àwọn ènìyàn, pàápàá orírun wọn gan-an. Iṣẹ́ yìí ṣe àtúpalẹ̀ àyọlò àṣàyàn orin ìbílẹ̀ Yorùbá Ìlọrin bíi dàdàkúàdà, orin agbè, orin bàlúù, orin àlùgétà/bẹ̀ǹbẹ́, sẹnwẹlẹ àti bẹ́ẹ̀ bẹ́ẹ̀ lọ. Tíọ́rì tí a lò fún àtúpalẹ̀ iṣẹ́ yìí ni Tíọ́rì Ìfojú-ìmọ̀-ìbára-ẹni-gbé-pọ̀-wò. Ìlànà tí a lò ni fífi ọ̀rọ̀ wá àṣàyàn díẹ̀ lára akọrin ìbílẹ̀ Ìlọrin lẹ́nu wò; àdàkọ orin wọn láti inú fọ́nrán àti àtúpalẹ̀ kókó tó jẹmọ́ èdè, àṣà àti ìtàn níbẹ̀. Iṣẹ̀ yìí ṣàfihàn pé tí ìtẹpẹlẹmọ́ àti ìpolongo bá wà fún gbígbọ́ àwọn orin ìbílẹ̀, ìlọsíwájú yóò máa bá èdè Yorùbá, tí àwọn èwe wa kò sì ní lè tẹ̀rì pátápátá sínú àwọn orin ìgbàlódé tàkasúfèé tó gbòde kan ní ọ̀rúndún yìí.
  • Loading...
    Thumbnail Image
    Item
    Ìlò-Èdè Nínú Àṣàyàn Ewì Àpilẹ̀kọ Tí Àwọn Òǹkọ̀wé-Bìnrin Yorùbá kọ: Olúyẹ́misí Adébọ̀wálé Àti Àrìnpé Adéjùmọ̀ Gẹ́gẹ́ Bí Àpẹẹrẹ
    (2021) Hakeem Olawale
    Àṣamọ̀ Púpọ̀ nínú àwọn òǹkọ̀wè-kùnrin ni wọ́n máa ń bu ẹnu àtẹ́ lu ìṣọwọ́lò-èdè àwọn òǹkọ̀wé-bìnrin pé ìlò-èdè wọn kò kúnjú òsùnwọ̀n tó. Iṣẹ́ àpilẹ̀kọ yìí wá gbìyànjú láti ṣe ìtúpalẹ̀ ìṣàmúlò-èdè nínú àṣàyàn ewì Olúyẹ́misí Adébọ̀wálé àti Àrìnpé Adéjùmọ̀ ní ìbámu pẹ̀lú ọ̀kọ̀ọ̀kan kókó-ọ̀rọ̀ wọn. Bákan náà ni a ṣe àfihàn àgbékalẹ̀ ewì àpilẹ̀kọ àwọn òǹkọ̀wé-bìnrin méjèèjì wọ̀nyìí ní ète àti jẹ́ kí á mọ̀ pé àparò kan kò ga jùkan lọ pẹ̀lú ìṣàmúlò èdè wọn. Ìlànà ìwádìí jẹ́ kíka àwọn ewì àpilẹ̀kọ Olúyẹ́misí Adébọ̀wálè àti Àrìnpé Adéjùmọ̀ lọ́rínkínniwín. A sì gbìyànjú láti ṣe ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwò pẹ̀lú àwọn akéwì wọ̀nyìí. A ṣe àdàkọ àti àtúpalẹ̀ ọ̀rọ̀ tí a gbà sílẹ̀ lẹ́nu wọn. Ọ̀pọ̀ ìwé tí ó wúlò fún iṣẹ́ yìí ni a yẹ̀wò ní àwọn ilé-ìkàwé kí iṣẹ́ yìí lè kúnjú òṣùwọ̀n. Tíọ́rì ìfojú-ìhun-wò ni a lò láti ṣe ìtúpalẹ̀ ìlò-èdè tí àwọn akéwì obìnrin wọ̀nyìí ṣàmúlò nínú ewì àpilẹ̀kọ wọn. Àtúpalẹ̀ yìí jẹ́ kí a rína rí ìlò-èdè tí àwọn akéwì méjèèjì wọ̀nyìí lò, èyí tó pèsè àlàyé tó gbòòrò fún wa láti gbé ọ̀kọ̀ọ̀kan àwọn akéwì náà lérí òṣùwọ̀n pẹ̀lú ìṣàmúlò-èdè àwọn òǹkọ̀wé-kùnrin akẹgbẹ́ wọn. A wá rí i dájú pé akéwì gidi ni wọ́n, wọn kìí ṣe aláriwo lásán. Àbájáde iṣẹ́ ìwádìí yìí jẹ́ kí a mọ̀ pé kò sí ìpèdè kan tó jẹ́ àdáni fún àwọn òǹkọ̀wé-bìnrin. Ní ìparí, iṣẹ́ yìí fìdí rẹ̀ múlẹ̀ pé kò sí bí ọkùnrin ṣe lè lo èdè tí àwọn obìnrin náà kò lè lò ó tí a bá ṣe àfiwé iṣẹ́-ọnà òǹkọ̀wé-bìnrin pẹ̀lú tí òǹkọ̀wé-kùnrin.
  • Loading...
    Thumbnail Image
    Item
    Ipa Ọ̀nà Ìbánisọ̀rọ̀ Ìgbàlódé lórí Ìtànkálẹ̀ àti Ìdàgbàsókè Orin Ìbílẹ̀ Ọlọ́mọ-Ọba Ìlọrin
    (2017) Hakeem Olawale
    Àṣamọ̀ Ọ̀kan pàtàkì lára orin ìbílẹ̀ Ìlọrin tó jẹ́ ajẹmábo-jẹ-máàfin ni orin Ọlọ́mọ-Ọba Ìlọrin jẹ́. A tilẹ̀ tún lè pè é ní ajẹmágbà nítorí pé àwọn àgbàlagbà obìnrin tó jẹ́ ẹbí àti ìyàwó ní ìdílé ọba Ìlọrin ló máa ń kọ ọ́. Lóòótọ́, a kò lè ṣàfẹ́kù ìkópa àwọn ọ̀ṣọ́ọ́rọ́ adélébọ̀ náà níbẹ̀ látì máa fojú sí i àti láti gbe orin náà, ṣùgbọ́n àwọn àgbàlagbà obìnrin tí ọjọ́ orí wọn ti lé ní ọgọ́ta ọdún ló wọ́pọ̀ nínú kíkọ orin náà. Àwọn tó jẹ́ ẹbí ọba Ìlọrin nìkan ni wọ́n ni orin yìí tí wọ́n sì fi máa ń yẹ́ ara wọn sí pàápàá jùlọ tí ọmọ ọba Ìlọrin kan bá ń ṣe ìgbéyàwó, yálà ó jẹ́ ọkùnrin tàbí obìnrin. A ṣàkíyèsí pé iṣẹ́ ìwádìí kò fi bẹ́ẹ̀ sí lórí orin yìí nítori pé wọn kìí gba àjòjì láàyè láti kópa níbẹ̀ débi tí yóò farabalẹ̀ máa ká eré wọn sílẹ̀. Èyí ló mú wa lọ gba ìyọ̀ǹda lati ààfin Ọba Ìlọrin gẹ́gẹ́ bí oníṣẹ́-ìwádìí, tí ó sì fún wa ní àǹfààní láti bá wọn kópa níbi òde orin wọn àti ṣíṣe ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwò tó kún. A ká wọn sínú ẹ̀rọ, a ya fọ́tò wọn, a sì tún rí orin wọn tó wà nínú fọ́nran díẹ̀ lára ìgbéyàwó tí wọ́n ti ṣe tẹ́lẹ̀ gbà láti ṣe àdàkọ fún ìtúpalẹ̀. Kókó pàtàkì tí iṣẹ́ yìí gùnlé ni àgbéyẹ̀wò àwọn iṣẹ́ pàtàkì tí wọ́n ń fi orin ólọ́mọ-ọba yìí jẹ́ láwùjọ Ìlọrin pẹ̀lú ipa pàtàkì tí onírúurú ọ̀nà ìbára-ẹni-sọ̀rọ̀ àti ti tọ́rọ́-fọ́n-kálé òde-òní ń kó lórí ìdàgbàsókè rẹ̀.Tíọ́rì Ajẹmọ́-àṣà-ìbílẹ̀ àti tíọ́rì Ìbára-ẹni-gbé-pọ̀ ni a fi ṣàtúpalẹ̀ iṣẹ́ yìí. Àbájáde iṣẹ́ yìí tànmọ́lẹ̀ sí i bó ṣe ṣe pàtàkì tó kí a máa mú ìgbélárugẹ bá àwọn nǹkan àṣà ìbílẹ̀ wa gbogbo nípasẹ̀ ìṣàmúlò àwọn ohun èlò ìgbàlódé oríṣìíríṣìí kí ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn nǹkan àjogúnbá wa má baà dohun ìgbàgbé, kí àmúgbòòrò àtí ìtẹ̀síwájú lè máa bá wọn, kó sì tún wúlò fún àwọn ìran tó ń bọ̀.
  • Loading...
    Thumbnail Image
    Item
    Ipa Ọ̀nà Ìbánisọ̀rọ̀ Ìgbàlódé lórí Ìtànkálẹ̀ àti Ìdàgbàsókè Orin Ìbílẹ̀ Ọlọ́mọ-Ọba Ìlọrin
    (2017) Hakeem Olawale
    Àṣamọ̀ Ọ̀kan pàtàkì lára orin ìbílẹ̀ Ìlọrin tó jẹ́ ajẹmábo-jẹ-máàfin ni orin Ọlọ́mọ-Ọba Ìlọrin jẹ́. A tilẹ̀ tún lè pè é ní ajẹmágbà nítorí pé àwọn àgbàlagbà obìnrin tó jẹ́ ẹbí àti ìyàwó ní ìdílé ọba Ìlọrin ló máa ń kọ ọ́. Lóòótọ́, a kò lè ṣàfẹ́kù ìkópa àwọn ọ̀ṣọ́ọ́rọ́ adélébọ̀ náà níbẹ̀ látì máa fojú sí i àti láti gbe orin náà, ṣùgbọ́n àwọn àgbàlagbà obìnrin tí ọjọ́ orí wọn ti lé ní ọgọ́ta ọdún ló wọ́pọ̀ nínú kíkọ orin náà. Àwọn tó jẹ́ ẹbí ọba Ìlọrin nìkan ni wọ́n ni orin yìí tí wọ́n sì fi máa ń yẹ́ ara wọn sí pàápàá jùlọ tí ọmọ ọba Ìlọrin kan bá ń ṣe ìgbéyàwó, yálà ó jẹ́ ọkùnrin tàbí obìnrin. A ṣàkíyèsí pé iṣẹ́ ìwádìí kò fi bẹ́ẹ̀ sí lórí orin yìí nítori pé wọn kìí gba àjòjì láàyè láti kópa níbẹ̀ débi tí yóò farabalẹ̀ máa ká eré wọn sílẹ̀. Èyí ló mú wa lọ gba ìyọ̀ǹda lati ààfin Ọba Ìlọrin gẹ́gẹ́ bí oníṣẹ́-ìwádìí, tí ó sì fún wa ní àǹfààní láti bá wọn kópa níbi òde orin wọn àti ṣíṣe ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwò tó kún. A ká wọn sínú ẹ̀rọ, a ya fọ́tò wọn, a sì tún rí orin wọn tó wà nínú fọ́nran díẹ̀ lára ìgbéyàwó tí wọ́n ti ṣe tẹ́lẹ̀ gbà láti ṣe àdàkọ fún ìtúpalẹ̀. Kókó pàtàkì tí iṣẹ́ yìí gùnlé ni àgbéyẹ̀wò àwọn iṣẹ́ pàtàkì tí wọ́n ń fi orin ólọ́mọ-ọba yìí jẹ́ láwùjọ Ìlọrin pẹ̀lú ipa pàtàkì tí onírúurú ọ̀nà ìbára-ẹni-sọ̀rọ̀ àti ti tọ́rọ́-fọ́n-kálé òde-òní ń kó lórí ìdàgbàsókè rẹ̀.Tíọ́rì Ajẹmọ́-àṣà-ìbílẹ̀ àti tíọ́rì Ìbára-ẹni-gbé-pọ̀ ni a fi ṣàtúpalẹ̀ iṣẹ́ yìí. Àbájáde iṣẹ́ yìí tànmọ́lẹ̀ sí i bó ṣe ṣe pàtàkì tó kí a máa mú ìgbélárugẹ bá àwọn nǹkan àṣà ìbílẹ̀ wa gbogbo nípasẹ̀ ìṣàmúlò àwọn ohun èlò ìgbàlódé oríṣìíríṣìí kí ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn nǹkan àjogúnbá wa má baà dohun ìgbàgbé, kí àmúgbòòrò àtí ìtẹ̀síwájú lè máa bá wọn, kó sì tún wúlò fún àwọn ìran tó ń bọ̀.
  • Loading...
    Thumbnail Image
    Item
    Ojú Àmúwayé Yorùbá Nípa Obìnrin Nínú Orin Sẹnwẹlẹ Ìlọrin
    (2022) Hakeem Olawale
    Àṣamọ̀ Ọ̀kan lára orin ìbílẹ̀ tó gbajúmọ̀ ní Ìlọrin ni orin sẹnwẹlẹ jẹ́. Àkóónú orin yìí kún fún ìkìlọ̀ ìwà, ẹ̀fẹ̀, ìpàkíyèsí, ìpanilẹ́rìn-ín, ọ̀rọ̀ nípa onírúurú ìṣesí obìnrin àti bẹ́ẹ̀ bẹ́ẹ̀ lọ. Nínú iṣẹ́ yìí, a ṣàgbéyẹ̀wò díẹ̀ lára àwọn orin sẹnwẹlẹ Alhaja Àwáwù Ìyáládùkẹ́ àti ti Múkáílà Ẹṣínrógunjó. Àfojúsùn wa ni láti wo àwọn àbùdá-àdámọ́ onírúurú tí obìnrin ní. Iṣẹ́ yìí túdìí ọ̀pọ̀ òkodoro nípa obìnrin bí wọ́n ṣe jẹ́ pàtàkì tó nínú àwùjọ àti kòṣeémání gẹ́gẹ́ bí iyọ̀ nínú ọbẹ̀ kó tó lè dùn. Ó sì tún jẹ́ ká mọ̀ bí ìwà ìbàjẹ́ kò ṣe jẹ́ nǹkan pàtàkì lójú irúfẹ́ àwọn obìnrin kan. Ìlànà ìwádìí ni gbígbọ́ àwọn orin ìbílẹ̀ sẹnwẹlẹ Ìyáládùkẹ́ lóríṣiríṣi àti ti Múkáílà Ẹṣínrógunjó. A ṣe àdàkọ wọn láti lè ṣe ọ̀rínkínniwín àtúpalẹ̀ àwọn kókó ajẹmóbìnrin inú wọn. A tún ṣe àmúlò àwọn ìwé àti àpilẹ̀kọ tó wúlò fún iṣẹ́ ìwádìí yìí. Tíọ́rì Ìmọ̀-Ìbára-ẹni-gbé-pọ̀ ni a lò láti ṣe àtúpalẹ̀ iṣẹ́ yìí nítorí pé ìbágbépọ̀ ẹ̀dá láàrin àwùjọ ló ń bí orin kíkọ. Àbájáde iṣẹ́ yìí fi hàn pé gẹ́gẹ́ bí ọ̀bẹ olójú-méjì ni àwọn obìnrin; iyẹn ni pé bí abiyamọ gidi obìnrin rere ṣe wà, tí wọ́n níwà ìtìjú, àfaradà, ìtẹpámọ́ṣẹ́, ìdáàbò bo ọkọ àti ọmọ náà ni ọ̀gọ̀ọ̀rọ̀ wọn jẹ́ oníwà-ìbàjẹ́ obìnrin, tí wọn kò léèpo lójú, alágbèrè, orogún ṣíṣe, olè jíjà àti bẹ́ẹ̀ bẹ́ẹ̀ lọ. Iṣẹ́ yìí fi ìdí òtítọ́ múlẹ̀ pé àwọn apohùn kò kùnà láti ṣe àfihàn àwọn obìnrin rere kí àwọn obìnrin akẹgbẹ́ wọn lè rí àwòkọ́ṣe rere lára wọn. Bákan náà ni wọn kò kùnà láti pàtẹ àwọn ìwà tí kò bójúmu tí àwọn obìnrin mìíràn ń hù nínú àwùujọ. A ṣe àkíyèsí pé, wọ́n ń ṣe àfihàn àwọn ìwà yìí láti fi kọ́ àwọn kọ̀lọ̀rọ̀sí abetí dídi nínú wọn lọ́gbọ́n ni.
  • Loading...
    Thumbnail Image
    Item
    Ojú Àmúwayé Yorùbá Nípa Obìnrin Nínú Orin Sẹnwẹlẹ Ìlọrin
    (2022) Hakeem Olawale
    Àṣamọ̀ Ọ̀kan lára orin ìbílẹ̀ tó gbajúmọ̀ ní Ìlọrin ni orin sẹnwẹlẹ jẹ́. Àkóónú orin yìí kún fún ìkìlọ̀ ìwà, ẹ̀fẹ̀, ìpàkíyèsí, ìpanilẹ́rìn-ín, ọ̀rọ̀ nípa onírúurú ìṣesí obìnrin àti bẹ́ẹ̀ bẹ́ẹ̀ lọ. Nínú iṣẹ́ yìí, a ṣàgbéyẹ̀wò díẹ̀ lára àwọn orin sẹnwẹlẹ Alhaja Àwáwù Ìyáládùkẹ́ àti ti Múkáílà Ẹṣínrógunjó. Àfojúsùn wa ni láti wo àwọn àbùdá-àdámọ́ onírúurú tí obìnrin ní. Iṣẹ́ yìí túdìí ọ̀pọ̀ òkodoro nípa obìnrin bí wọ́n ṣe jẹ́ pàtàkì tó nínú àwùjọ àti kòṣeémání gẹ́gẹ́ bí iyọ̀ nínú ọbẹ̀ kó tó lè dùn. Ó sì tún jẹ́ ká mọ̀ bí ìwà ìbàjẹ́ kò ṣe jẹ́ nǹkan pàtàkì lójú irúfẹ́ àwọn obìnrin kan. Ìlànà ìwádìí ni gbígbọ́ àwọn orin ìbílẹ̀ sẹnwẹlẹ Ìyáládùkẹ́ lóríṣiríṣi àti ti Múkáílà Ẹṣínrógunjó. A ṣe àdàkọ wọn láti lè ṣe ọ̀rínkínniwín àtúpalẹ̀ àwọn kókó ajẹmóbìnrin inú wọn. A tún ṣe àmúlò àwọn ìwé àti àpilẹ̀kọ tó wúlò fún iṣẹ́ ìwádìí yìí. Tíọ́rì Ìmọ̀-Ìbára-ẹni-gbé-pọ̀ ni a lò láti ṣe àtúpalẹ̀ iṣẹ́ yìí nítorí pé ìbágbépọ̀ ẹ̀dá láàrin àwùjọ ló ń bí orin kíkọ. Àbájáde iṣẹ́ yìí fi hàn pé gẹ́gẹ́ bí ọ̀bẹ olójú-méjì ni àwọn obìnrin; iyẹn ni pé bí abiyamọ gidi obìnrin rere ṣe wà, tí wọ́n níwà ìtìjú, àfaradà, ìtẹpámọ́ṣẹ́, ìdáàbò bo ọkọ àti ọmọ náà ni ọ̀gọ̀ọ̀rọ̀ wọn jẹ́ oníwà-ìbàjẹ́ obìnrin, tí wọn kò léèpo lójú, alágbèrè, orogún ṣíṣe, olè jíjà àti bẹ́ẹ̀ bẹ́ẹ̀ lọ. Iṣẹ́ yìí fi ìdí òtítọ́ múlẹ̀ pé àwọn apohùn kò kùnà láti ṣe àfihàn àwọn obìnrin rere kí àwọn obìnrin akẹgbẹ́ wọn lè rí àwòkọ́ṣe rere lára wọn. Bákan náà ni wọn kò kùnà láti pàtẹ àwọn ìwà tí kò bójúmu tí àwọn obìnrin mìíràn ń hù nínú àwùujọ. A ṣe àkíyèsí pé, wọ́n ń ṣe àfihàn àwọn ìwà yìí láti fi kọ́ àwọn kọ̀lọ̀rọ̀sí abetí dídi nínú wọn lọ́gbọ́n ni.
  • Loading...
    Thumbnail Image
    Item
    Oral Traditions and Preservations of Cultural Heritage
    (2023) Hakeem Olawale
    It was pointed out by Ìṣọ̀lá (2010) that culture is God's own way of organizing people all over the world in cohesive groups, each around a language, with its own peculiar skills and knowledge…A group's language makes effective and independent operation possible. Moreover, Bọ́láńlé Awẹ́ in Adéẹ̀kọ́ (2001) opined that historians of non-literate societies should view oral traditions as valuable sources for chronicling the evolution of African social and cultural consciousness, because in societies without permanent archives, creative orature captures the mentalities of their milieu of production and consumption .This paper therefore discusses the relevance of oral traditions as a medium whereby multifarious African languages can be preserved and documented if tactically utilized. So far language is a culture dictionary, or rather its encyclopedia, its issues cannot be underestimated or viewed with a nonchalant attitude in society. To preserve and document African languages to prevent them from going into extinction, oral traditions play prominent roles. This paper explicates the roles of oral traditions to revive or save the endangered languages and for the preservation of cultural heritage. Africa is home to about 2,000 of the 6,000 languages spoken in the world today and many of these languages are used mostly in the oral or unwritten form. It plays the role of recalling the past through its complexity. As mentioned earlier, the aim of this paper is to explicate the authenticity of oral traditions towards the preservation, documentation and revival of African languages and cultural heritage. Keywords: Traditions, Orature, Extinction, Cultural Heritage, Preservations.
  • Loading...
    Thumbnail Image
    Item
    Oral Traditions and Preservations of Cultural Heritage
    (2023) Hakeem Olawale
    It was pointed out by Ìṣọ̀lá (2010) that culture is God's own way of organizing people all over the world in cohesive groups, each around a language, with its own peculiar skills and knowledge…A group's language makes effective and independent operation possible. Moreover, Bọ́láńlé Awẹ́ in Adéẹ̀kọ́ (2001) opined that historians of non-literate societies should view oral traditions as valuable sources for chronicling the evolution of African social and cultural consciousness, because in societies without permanent archives, creative orature captures the mentalities of their milieu of production and consumption .This paper therefore discusses the relevance of oral traditions as a medium whereby multifarious African languages can be preserved and documented if tactically utilized. So far language is a culture dictionary, or rather its encyclopedia, its issues cannot be underestimated or viewed with a nonchalant attitude in society. To preserve and document African languages to prevent them from going into extinction, oral traditions play prominent roles. This paper explicates the roles of oral traditions to revive or save the endangered languages and for the preservation of cultural heritage. Africa is home to about 2,000 of the 6,000 languages spoken in the world today and many of these languages are used mostly in the oral or unwritten form. It plays the role of recalling the past through its complexity. As mentioned earlier, the aim of this paper is to explicate the authenticity of oral traditions towards the preservation, documentation and revival of African languages and cultural heritage.
  • No Thumbnail Available
    Item
    Orin Dàdàkúàdà Gẹ́gẹ́ Bí Atọ́nà Ìgbáyégbádùn Láwùjọ
    (2025) Hakeem Olawale
    Kókó pàtàkì tí iṣẹ́ yìí dá lé lórí ni àgbéyẹ̀wò ìwúlò orin dàdàkúàdà tó jẹ́ ọ̀kan lára orin ìbílẹ̀ Yorùbá ní Ìlọrin nílẹ̀ Nàìjíríà gẹ́gẹ́ bí atọ́ka ìgbáyégbádùn, ìwà ọmọlúàbí àti ìbágbépọ̀ àlàáfíà láwùjọ wa. Iṣẹ́ yìí ṣàfihàn ìwúlò orin lápapọ̀ nípa onírúurú iṣẹ́ tí a ń fi orin jẹ́ láwùjọ ọmọ ènìyàn. Ó sì ṣe àgbéyẹ̀wò díẹ̀ lára àkóónú orin dàdàkúàdà lára àwọn òjìnmí elérée dàdàkúàdà nílẹ̀ Ìlọrin bíi Jáígbadé Àlàó, Odòlayé Àrẹ̀mú, Ọmọékeé Àmọ̀ó àti Àrẹ̀mú Òsé gẹ́gẹ́ bí àwògbè. Orin dàdàkúàdà lánàá, lónìí àti lọ́la. Àwọn olórin ti a yàn láàyò yìí ni ìpèdè Yorùbá wọn jinlẹ̀ nínú àwọn àwo orin wọn, tó sì kún fún ọ̀pọ̀lọpọ̀ ọgbọ́n àti òye tí ènìyàn lè ṣàmúlò láti tún ọmọlúàbí rẹ̀ ṣe nípa ìhùwàsí èyí tó lè ṣe okùnfà ìbágbépọ̀ àlàáfíà fún ìtẹ̀síwájú àwùjọ. Lóòótọ́ ni àwọn orin mìíràn wà tó jẹ́ ti ìbílẹ̀ Ìlọrin tí a mọ̀ wọ́n mọ̀ bí orin bàlúù, orin wákà, orin kèǹgbè, orin kàkàkí àti bẹ̀ǹbẹ́, orin ọlọ́mọ́-ọba, orin agbè àti bẹ́ẹ̀ bẹ́ẹ̀ lọ, ṣùgbọ́n láàrin obì, ọ̀tọ̀ làá yọ oófúà sí ni ọ̀rọ̀ orin dàdàkúàdà. Iṣẹ́ yìí wa ṣe àtúpalẹ̀ àwọn kókó díẹ̀ nínú àkóónú orin àwọn àṣàyàn olórin dàdàkúàdà náà. Tíọ́rì ìmọ̀-ìbárá-ẹni-gbé-pọ̀ ni a lò láti ṣe àtúpalẹ̀ àwọn kókó atáwùjọṣe tí a ṣàmúlò nínú àwọn orin náà, nítorí pé ìbágbépọ̀ ẹ̀dá wà lára kókó pàtàkì tó ń bí orin kíkọ nínú àwùjọ. Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé ayé ti di ayé ọ̀làjú báyìí tí ọ̀pọ̀lọpọ̀ ìkọkúkọ orin ti gbòde kan, èyí ni ó fà á tí iṣẹ́ yìí fi ṣàfihàn orin dadakúàdà gẹ́gẹ́ bí ọ̀tọ̀lórìn tí gbígbọ́ rẹ̀ kún fún ọgbọ́n, ìmọ̀ àti òye èyí tó lè ṣàǹfààní fún wa nípa híhu ìwà ọmọlúàbí, ìgbáyégbádùn àti ìbágbépọ̀ àlááfíà, kí àwọn ènìyàn àwùjọ sì má baà gbàgbé ogún rere tó wà nílẹ̀ nínú orin àti àwọn ìpohùn ìbílẹ̀ wa gbogbo. Kókó ọ̀rọ̀: Dàdàkúàdà, Ìgbáyégbádùn, Ọ̀rínkíniwín, Ọmọlúàbí, Àwògbè, Ibágbépọ̀ Àlàáfíà.
  • No Thumbnail Available
    Item
    Philosophy of Ọbáfẹ́mi Awólọ́wọ̀ and Nation Building202
    (2024) Hakeem Olawale
    It is noteworthy that Late Chief Jeremiah Oyèníyì Ọbáfẹ́mi Awólọ́wọ̀ is one of the foremost Elder Statesman whose philosophy of life and actions contributed immensely to the development of the country, Nigeria. Despite his demise, his contributions in the history of Nigeria will forever remain commendable because of the positive impacts of his visionary, developmental political philosophy and selfless service to humanity in his social, educational, family, professional and political life. This paper explores multifarious aspects of Ọbáfẹ́mi Awólọ́wọ̀’s contributions towards the attainment of Nigeria’s independence ; his philosophy of Free Education in the Western Region; his economic policy for the Government; Political life and many others. The paper concludes that if Ọbáfẹ́mi Awólọ́wọ̀’s developmental and selfless philosophy of life is carefully explored, immitated and practiced, most especially by the political class of nowadays, our dear country will achieve greatness and be freed from financial reckless and embezzlement of the highest order the country is presently battling with.
  • No Thumbnail Available
    Item
    The Philosophy of Ọbáfẹ́mi Awólọ́wọ̀ and Nation Building
    (2025) Hakeem Olawale
    It is noteworthy that Late Chief Jeremiah Oyèníyì Ọbáfẹ́mi Awólọ́wọ̀ is one of the foremost elder statesman whose philosophy of life and actions contributed immensely to the development of the country, Nigeria. Despite his demise, his contributions to the building of Nigeria will forever remain commendable because of the positive impacts of his visionary, developmental political philosophy and selfless service to humanity in his social, educational, family, professional and political life. This paper explores multifarious aspects of Ọbáfẹ́mi Awólọ́wọ̀’s contributions towards the attainment of Nigeria’s independence; his philosophy of Free Education in the Western Region; his economic policy for the Government; Political life and many others. The paper concludes that if Ọbáfẹ́mi Awólọ́wọ̀’s developmental and selfless philosophy of life is carefully explored, imitated and practiced, most especially by the political class of nowadays, our dear country will achieve greatness and be freed from financial reckless and embezzlement of the highest order the country is presently battling with.
  • Loading...
    Thumbnail Image
    Item
    Traditional Songs as Catalyst for Integration: A Study of Selected Ìlọrin Songs
    (2107) Hakeem Olawale
    Traditional singers in African societies are like historians in many cases. Themes and allussions in their renditions reveal a lot of facts which in turn proffer solutions to many issues. This is in line with Bọ́láńlé Awẹ́’s opinion cited in Adéẹ̀kọ̀ that: “Historians of non-literate societies should view oral traditions as valuable sources for chronicling the evolution of African social and cultural consciousness, because, in societies without permanent archives, creative oratures do capture the mentalities of their milieu of production and consumption” (2001, p.181). Okafor (2005) locates the authenticity of music as a mirror through which a society is viewed when he says: “ Music is a human activity as part of human existence. This existence comprises and implicates various activities in an environment. The totality is what is closely defined as culture... It is well known that man in his different environment produces different cultures.Consequently, music will have different purposes, characteristics and implications in different cultures and environment. In African culture, music is an entity rather than a mere mental creation or conception. It reflects and interpretes the man in a specific environment and is often the key, which opens the gate to spiritual, mental, emotional, psychological, social and mystic realms (pp.87-88). The above opinion of Okafor refers to the prominent roles African music play in virtually all aspects of the society.Music and society are interwoven because music is all about what has happened and is also presently happening in the society.This is because the interactions of people in the society bring about what artistes compose into songs.
  • Loading...
    Thumbnail Image
    Item
    Traditional Songs of Ìlọrin: Enacting Identities, History and Cultural Memories
    (2017) Hakeem Olawale
    Ìlọrin is a distinct community and a melting pot where people of diverse ethnic and cultural identities came together to form a settlement from the 17th century. These ethnic groups include Yorùbá, Haúsá, Fúlàní, Núpé, Kànnìké, Kéńbérí, Bàrùbá, and Malians¸ Arabs among others. However, despite this ethnic and cultural diversities and the fact that Fúlàní hold political authority in Ìlọrin, Yorùbá language is the lingua franca of this community. How these ethnic groups find their voices and articulate their historical and cultural identities within this unified framework becomes a source of concern. As a response to this concern, traditional songs of Ìlọrin like dàdàkúàdà, bàlúù, agbè, wákà, kèǹgbè, orin ọlọ́mọ-ọba Ìlọrin, among others sung in Yorùbá language become a site of contestation of ethnic and cultural identities. The focus of this paper is to analyze Ìlọrin traditional songs as they portray and contest ethnic identities, reconstruct history and revitalize cultural memories of indigenes. The paper argues that given such a diverse ethnic and cultural origins, performance of Ìlọrin traditional songs become a reminder of family histories, origins, political structure, hegemonic influences, myths, legends Islamisation of Ìlọrin and a way of ensuring harmony and bridging generational gaps among the various groups in a state that is dubbed ‘state of harmony’.
  • Loading...
    Thumbnail Image
    Item
    Traditional Songs of Ìlọrin: Enacting Identities, History and Cultural Memories
    (2017) Hakeem Olawale
    Ìlọrin is a distinct community and a melting pot where people of diverse ethnic and cultural identities came together to form a settlement from the 17th century. These ethnic groups include Yorùbá, Haúsá, Fúlàní, Núpé, Kànnìké, Kéńbérí, Bàrùbá, and Malians¸ Arabs among others. However, despite this ethnic and cultural diversities and the fact that Fúlàní hold political authority in Ìlọrin, Yorùbá language is the lingua franca of this community. How these ethnic groups find their voices and articulate their historical and cultural identities within this unified framework becomes a source of concern. As a response to this concern, traditional songs of Ìlọrin like dàdàkúàdà, bàlúù, agbè, wákà, kèǹgbè, orin ọlọ́mọ-ọba Ìlọrin, among others sung in Yorùbá language become a site of contestation of ethnic and cultural identities. The focus of this paper is to analyze Ìlọrin traditional songs as they portray and contest ethnic identities, reconstruct history and revitalize cultural memories of indigenes. The paper argues that given such a diverse ethnic and cultural origins, performance of Ìlọrin traditional songs become a reminder of family histories, origins, political structure, hegemonic influences, myths, legends Islamisation of Ìlọrin and a way of ensuring harmony and bridging generational gaps among the various groups in a state that is dubbed ‘state of harmony’.
  • Loading...
    Thumbnail Image
    Item
    Women in Obasá’s Poetry
    (2021) Ayoola Oladunnke Aransi; Hakeem Olawale
    Obasá’s creativity cuts across virtually all aspects of Yorùbá socio-cultural ̣ settings and his works have attracted the attention of various scholars. It is evident that his poems are laden with topical issues that are of national interest. Most of his works, as described by previous scholars, are based on his love for and interest in Yorùbá language, social values, language, style, cultural practices, and the recovery endangered Yoruba oral art (Babalolá 1971, ̣ 1973; Olábimtán 1974a, 1974b; Ògúnsínà 1980; O ̣ látúnji 1982; Akínye ̣ mí 1987, ̣ 1991, 2017; and Nnodim 2006). Tis essay focuses on the representation of women in Obas ̣ á’s poetry, a topic that has not been given adequate attention. ̣ The essay attempts a close reading of Obas ̣ á’s poems within the Feminism and ̣ womanism theoretical frameworks. The research reveals that the representation of women in the poetry of Obasa did not go beyond the stereotypical and derogatory portrayal of women among the Yoruba.
  • «
  • 1 (current)
  • 2
  • »

KWASU Library Services © 2023, All Right Reserved

  • Cookie settings
  • Send Feedback
  • with ❤ from dspace.ng